Home / Art / Àṣà Oòduà / Akeredolu bó̩ nínú àjàgà covid-19
Akeredolu

Akeredolu bó̩ nínú àjàgà covid-19

Akeredolu bó̩ nínú àjàgà covid-19

Ajakale arun coronavirus ti n pa eni kukuru, to n pa eni giga, ti ko mo olowo yato fun talaka, ko mo oba bee ni ko mo ijoye, ko ki n ja ija elesinmesin, ko si ohun to kan an pelu eleyameya.


Ajakale ohun naa lo ko lu odidi bii gomina mejo ni orileede yi, ni eyi ti Arakunrin Rotimi Akeredolu wa ninu won. Ose to koja lo kede funra re pe ayewo oun gbe arun coronavirus jade. Gomina yii ba lo fun iwosan, o bere si ni sise ofiisi nile.


Gomina yii naa lo tun kede ni irole oni pe ki a ba oun dupe nipa esi ayewo to tun jade lonii ti o si gbee pe aisan naa ti kuro ni ago ara Gomina Akeredolu.

Yínká Àlàbí

About AbubakarMuhd

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...