Home / Art / Àṣà Oòduà / O̩ló̩run sì máa gbè̩san ikú bàbá mi – O̩mo̩ o̩ko̩ olóyún
oko oloyun

O̩ló̩run sì máa gbè̩san ikú bàbá mi – O̩mo̩ o̩ko̩ olóyún

Olorun si maa gbesan iku baba mi – Omo ojo Oloyun
Ojo ketalelogun osu kin-in-ni odun yii ni awon adiha-Moran kan lo yinbon pa Alhaji Fatai Yusuf ti gbogbo eniyan mo si oko oloyun.


Lati igba naa ni awon olopaa ti n se iwadii awon to se ise ibi naa.
Akoroyin iwe iroyin PUNCH lo se alabapade Kehinde Yusuf to je omo oloogbe naa.

Kehinde soro ile kun, o ni ju gbogbo re lo, o da oun loju to ada pe Eledua si maa gbesan iku baba oun lara awon eniyan buruku naa.


O ni baba oun ko ki n ba eniyan ja bee ni ko ki n ba eniyan ta. O ni jeje ni baba yii maa n lo, ti o si maa n mura si bi okowo re se maa gberu sii.
Kehinde ni oun gege bi omo Naijiria ko reti abajade lodo awon olopaa sugbon oun ni igbagbo ninu Olorun.

O tun ni ebi oun gan-an ko gbe awon to pa baba naa sokan bi ko se bi awon se maa te siwaju. Bi awon se maa rii pe eto eko oun ati awon aburo oun ko duro nitori pe awon po die.


O ni ko rorun fun mama oun nikan lati to ono mewaa sugbon awon ni igbagbo ninu Olorun. O ni ipade lorisirisii ti n lo lati le foju to gbogbo idasile baba oun naa. O ni awon ko fe ki okankan parun rara.


O ni ara eko ti baba awon fi ko awon ni ki awon tepa mose nitori pe atelewo eni ko ki n tan ni je. O ni baba naa ni ki awon tun sun mo Olorun, ki awon maa ke pee ni gbogbo igba.


Kehinde ni ko si eni ti iku baba naa ko dun ninu ebi oun, o kan je wi pe o dun oun gan-an ni nitori pe oun ni oun di eru baba naa ti oun si gbe si inu moto won, o ni sadede ni iroyin buruku naa kan oun lara ni ojo keji pe won ti yinbon pa baba naa.

O ni bi ala lo ko ri ki awon ipe to maa wole lorisiirisii ti awon eniyan si tun bere si ni wo wa si ile awon.


Kehinde ni eyi je ki o pe die ki oun to le pada si ile-iwe nitori pe oun kan sare wale ni ireti ati pada kiakia ki isele naa to sele.

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...