Home / Art / Àṣà Oòduà / Ọ̀ràn dé! Alárùn coronavirus di méjì ní Nàìjíríà
coronavirus

Ọ̀ràn dé! Alárùn coronavirus di méjì ní Nàìjíríà

Lara ayewo ti ijoba apapo ati awon ajo NCDC (Nigeria Centre for Disease Control) n se pelu awon ti won ba arakunrin ara orileede Italy wo baalu ati oko po. Won n se ayewo yii naa pelu awon ti won jo se ipade ni ilu Ewekoro to wa ni ipinle Ogun.

Ileese Lafarge Cement Plant Plc ni ipade naa ti waye. Eyi lo mu ki ijoba apapo ati ti ipinle Ogun pelu Eko pa imo po lati maa se ayewo gbogbo awon to ni asepo pelu arakunrin yii lati ojo keedogbon osu keji odun yii.
Dokita Osagie Ehanire jeri si oro naa pe awon ti ri elomiran to ko kokoro naa lati odo okunrin naa.

Dokita yii si tun fi gbogbo omo Naijiria lokan bale pe ko si ewu Kankan, ki onikaluku maa lo si ibi ise oojo re.

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...