Home / Art / Culture / Àwo̩n S̩ó̩ò̩sì bè̩rè̩ ìjó̩sìn l’Abuja lónìí
catholic church

Àwo̩n S̩ó̩ò̩sì bè̩rè̩ ìjó̩sìn l’Abuja lónìí

Àwo̩n S̩ó̩ò̩sì bè̩rè̩ ìjó̩sì l’Abuja lónìí
Yínká Àlàbí

O le ni osu meji bayii ti ijoba apapo ti fofin de Soosi ati Mosalasi. Ijoba ni ki onikaluku maa josin ni ile won, ijoba ni ko si ibi ti Olorun ko si ati wi pe Olorun sun mo wa ju isan orun wa lo.

Eyi lo mu ki gbogbo ile ijosin wa ni titi pa. Ijeeta ojo jimo, ojo karun-un, osu kefa yii ni ijoba apapo ni ki awon Mosalasi gbogbo ni ilu Abuja bere ijosin won pada. Koda Aare Mohammadu Buhari naa ba won kirun Jimo ni Aso Rock lojo naa.


Oni ojo keje, osu kefa yii kan naa ni ijoba ni ki awon Soosi bere isin won pada.

Gbogbo ofin ti ijoba apapo ati ajo NCDC gbe sile ni awon Mosalasi ati Soosi n tele koda awon elesin kirisiteeni ba de bi wi pe, won n foruko sile notori ti nnkan ti won ko ro ba sele, eyi maa rorun lati le to ile awon to josin ni ojo naa lo.

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

nigerian police

Họ́wù! Àgọ́ ọlọ́pàá ni wọ́n tí fọmọ odó lu èèyàn méjì pa

Họ́wù! Àgọ́ ọlọ́pàá n wọ́n tí fọmọ odó lu èèyàn méjì pa Ará kò níí tán nílé alárà láé láé. À bí kínni kí á tí wí pẹ̀lú bí èèyàn méjì ti kú lẹ́yìn tí ọlọ́pàá kan fi ọmọ odó lu ọ̀dọ́ mẹ́ta fún pé wọ́n jí adìẹ. Ẹnìkẹta, Abdulwahab Bello, nìkan ni ó yè. Ṣùgbọ́n, ó fi ara gba ọgbẹ́, tí egungun rẹ̀ sì kán, lẹ́yìn tí ọlọ́pàá náà lù wọ́n ní àgọ́ ọlọ́pàá kan ní Ìpínlẹ̀ Bauchi. Abdulwahab ...