Home / Art / Àṣà Oòduà / E̩ tu èékánná lára S̩owore – Ilé-e̩jó̩
sowore

E̩ tu èékánná lára S̩owore – Ilé-e̩jó̩

Ile-ejo giga to fi ikale si ilu Abuja lo pase fun ijoba apapo pe ki won yokun lorun Ogbeni Omoyele Sowore.
Sowore ni o n gbimo lati se iwode Kan to maa mi ilu titi. Lati igba naa ni ijoba apapo ti fi owo sinkun ofin mu u.
Ogbeni Sowore ti lo ojo marundinlaadota ninu ayanran awon olopaa bayii.
Agbejoro agba to n gbejo fun Sowore, Alagba Femi Falana ni kia ni oun maa ko iwe ti ile-ejo ni ki awon ko ki won le yonda re fun awon ebi re ni oni ojo kerinlelogun, osu kesan-an yii.
Ile-ejo ni ki awon agbofinro gba gbogbo iwe irinna Sowore, ki Alagba Falana si mo daju pe orun oun lo wa. Ile-ejo ni igbakuugba ni awon le pee lati wa jejo.

Main

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Yemoja

Celebrating the Orisa Yemoja

Each year, the Oodua people in Nigeria give thanks to Yemoja, Orisa of the river and mother of all other Oodua Orisa. It is an important way for us to remember and celebrate our traditional roots and beliefs. Ibadan, Oyo State, Nigeria – During the annual festival to celebrate Yemoja, the Orisa of the river, the afternoon begins with music, dance and prayers. You will find 401 Orisa– called ÒRÌSÀ in the Oodua tradition – each representing a force of nature. ...