Home / Art / Àṣà Oòduà / Èàkàn ẹgbẹ́ òṣèlú APC mií Lanre Rasak dágbére fáyé
ẹgbẹ́ òṣèlú APC

Èàkàn ẹgbẹ́ òṣèlú APC mií Lanre Rasak dágbére fáyé

Èàkàn ẹgbẹ́ òṣèlú APC mií Lanre Rasak dágbére fáyé

Èèkàn ẹgbẹ́ òṣèlú APC nípìńlẹ̀ Èkó, Lanre Razak ti jáde láyé lẹ́ni ọdún mẹ́rìnléláàdọ́rin.

Kí ikú ó pajú èèyàn dé lójijì ti wá fẹ́ ẹ̀ kúrò ní ń tí wọ́n kíìyàn yàn pé Ọlọ́run má jẹ́ á rírú ẹ̀ mọ́, bí ó se pé ká sá maa sọ fún Ọlọ́run pé kọ́dún ó jìnà síra wọn.

Ìṣẹ́jú ìṣẹ́jú sáà ni ẹ̀mí ń bọ́ lára gbogbo n tí Aláwùràbí dá, tèèyàn ló kàn wá jù ,la ṣe ń gbarata.
Ọkàn pàtàkì tún ni ti
Ọ̀gbẹ́ni Lanre Razak yìí tó papòdà lọ́jọ́ Àbámẹ́ta ọjọ́ kẹẹ̀ẹ́dógún oṣù kẹjọ ọdún 2020 yìí ,lẹ́yìn àìsàn ráńpẹ́.

Nígbà ayé rẹ̀, Ọ̀gbẹ́ni Razak wà nínú Ìgbìmọ̀ tó ń gba Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkó lámọ̀ràn.

Ọ̀gbẹ́ni Rasak kọ́kọ́ fi èròńgbà rẹ̀ hàn láti díje fún ipò Sẹ́nétọ̀í lẹ́kùn ìlà oòrùn ìpínlẹ̀ Èkó kí ó tó yọwọ́ níbẹ̀ ṣaájú ìbò abẹ́lé.

Ọjọ́ Àìkú ọjọ́ kẹrìndínlógún oṣù kẹjọ yìí ni wọn yóó ṣin Ọ̀gbẹ́ni Rasak ní Ìlànà ẹ̀ṣìn mùsùlùmí.

Fẹ́mi Akínṣọlá

About AbubakarMuhd

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

aspirant

‘Peter Obi Is Not Popular In Nasarawa’ – Gov Sule Explains Why 2023 Presidency Is Between Tinubu And Atiku

Governor of Nasarawa state, Abdullahi Sule has disclosed that the 2023 presidential election is a two-horse race between the All Progressives Congress (APC) and the Peoples Democratic Party (PDP). This was made known by the governor while dismissing the chances of Labour Party (LP) Presidential candidate, Peter Obi, and the New Nigeria Peoples Party (NNPP), Rabiu Kwankwaso in the election. Sule said they missed their chance to be strong contenders in the 2023 presidential election when they failed to come ...