Home / Art / Àṣà Oòduà / El- Rufai bá e̩bí ènìyàn 51 ké̩dùn

El- Rufai bá e̩bí ènìyàn 51 ké̩dùn

El- Rufai bá e̩bí ènìyàn 51 ké̩dùn
Nnkan buruku sele ni ilu Giwa ati Igali ni oru ojo aiku moju ojo Aje.
Awon adihamora ni won tun ya bo awon ilu ati abule ni ipinle Kaduna ti won si bere si pa awon eniyan ibe, won si tun dana sun ile ati awon nnkan ini won miiran.

Gomina ipinle naa, Nasir El- Rufai se abewo si awon ilu naa lonii, o si ba won kedun gidi nipa awon emi to sonu.
Aare Mohammadu Buhari naa ranse ibani kedun si ipinle naa nipa awon eniyan ti won padanu.

Ki Eledua ba wa dawo aburu duro.

Ìròyìn láti o̩wó̩ Yínká Àlàbí

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...