Home / Art / Àṣà Oòduà / Ènìyàn mó̩kàndínlógójì ti ní àsepò̩ pèlú alárùn coronavirus l’Ogun
coronavirus

Ènìyàn mó̩kàndínlógójì ti ní àsepò̩ pèlú alárùn coronavirus l’Ogun

Ènìyàn mó̩kàndínlógójì ti ní àsepò̩ pèlú alárùn coronavirus l’Ogun
Ìròyìn láti o̩wó̩ Yínká Àlàbí


Iberu bojo ti po gan-an ni ipinle Ogun bayii, paapaa julo lati igba ti ayewo ti fihan pe alarun buruku kan ti wo orileede yii lati orileede Italy.
Lati igba naa ni ijoba ti bere si nii se iwadii gbogbo ibi ti arakunrin naa de ki o to di pe aisan naa daa gunle.

italy corona virus


Won ni ilera ti yara n sele si arakunrin naa, amo ayewo to gbopan gbodo waye pelu awon to ba se ipade ni Ewekoro to wa ni ipinle Ogun.
Won ni ayewo gbodo wa pelu eni to fi moto gbee lati papako ofurufu, won ni ayewo gbodo waye lori awon ti won jo wo baalu de ipinle Eko ati bee bee lo.


Elegbe gbogbo ipinle ni o ti gbaruku ti imurasile arun buruku naa ki o maa baa ba won ni ojiji. Iwadii ko tii fihan boya awon eniyan yii ti ko arun tabi won ko koo.

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...