Home / Art / Àṣà Oòduà / Ènìyàn O̩gbò̩n Ti Lùgbàdì Coronavirus Ni Naijiria
corona virus

Ènìyàn O̩gbò̩n Ti Lùgbàdì Coronavirus Ni Naijiria

Ènìyàn o̩gbò̩n ti lùgbàdì coronavirus ni Naijiria
Ìròyìn láti o̩wo̩ Yínká Àlàbí

Afi ki Eledua maa ko wa yo ni orileede yii. Bi ere bi awada, ajakale arun kogboogun (covid-19) ti mu eniyan ogbon di asiko ti a n ko iroyin yii jo ni ojo aiku, ojo kejilelogun, osu keta odun 2020.

Gege bi ajo to n mojuto eto ilera naa, N C D C, (Nigeria centre for disease control) se gbee sita.
Won ni mejilelogun lo yoju ni ipinle Eko, merin ni Abuja, meji ni Ogun, okan ni Oyo nigba ti okan to ku naa wa lati Ipinle Ekiti.

Gbogbo ileewe lo ti fere wa ni titi pa, opo osise lo ti wa nile sibe won ni ki a je ki imototo wa po sii lasiko yii.

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...