Home / Art / Àṣà Oòduà / Ọba mẹ́wàá, ìgbà mẹ́wàá
sanusi

Ọba mẹ́wàá, ìgbà mẹ́wàá

Awon onpitan wu itan Emir Kano ana jade. Won ni oro re dabi egun ti baba baba re ti se sile. Won ni odun 1963 ni ede aiyede waye laare Emir Mohammed Sanusi to je baba eni ti gomina yo ni ana yii pelu Amenh Oboni ti ilu Igala.


Rogbodiyan yii naa ni o yo baba Sanusi ana kuro lori oye. Odun ketadinlogota naa ree bi ana, ti gomina Gaduje tun yo Emir Sanusi kuro bi eni yo jiga. Loju ese naa ni won fi omo Aminu Ado Bayero dipo re.


Orisiirisii esun ni ijoba ipinle Kano fi kan Emir Sanusi, won ni o se owo rogunrogun kan maku maku ti ko si alaye gidi Kankan lori re. Won ni ko ki n gboro si ijoba ipinle naa lenu rara. Gbogbo eyi ni won ko po ti ijoba ipinle naa fi ni osuwon re ti kun.

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...