Home / Art / Àṣà Oòduà / Ọ̀nà Jìbìtì
Ọ̀nà Jìbìtì

Ọ̀nà Jìbìtì

Bi ara ipede Radio Naigeria O.Y.O ni aye atijo, won ni, “Ifunra loogun agba, pasa ko funra, o ja sina, aja ko funra, aja jin, ti onile naa ko ba funra, ole ni yoo ko lo”. Eyi ni o difa fun gbogbo awa ti a maa n gbe moto lo si ibi inawo.


Ara iwa jibiti ibe ni ki awon kan lo ba adari eto ti gbogbo eniyan mo si M.C. Won a ni ki o polongo nomba moto jade, ki eni to nii le wa tun wa si ibi to dara.


Igba ti eni naa ba de ibe lo maa dede ri awon kan ti won ti go dee pelu ibon. Won si maa ni ki o ko gbogbo owo ati awon nnkan miiran to ba lowo lori fun awon loju ese.


Opo to ba se agidi maa n sabaa fara gba ogbe ti won ko ba ba isele naa lo.
Iwe IROYIN OWURO wa n gba wa niyanju pe ti iru ikede bee ba sele, ki onimoto ma tete lo, ti o ba si lo ki o ma se da lo. E ma se je ki a dabii “f’Olorunso to n fokun ogede gope”.

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...