Home / Art / Àṣà Oòduà / “Efon ti n fa kokoro Zika wa ni Naijiria, kosi ti gboogun”- Minisita Ilera
efon-zika

“Efon ti n fa kokoro Zika wa ni Naijiria, kosi ti gboogun”- Minisita Ilera

Minisita fun eto ilera, Ojogbon Isaac Adewole, ti se idaniloju alaye wi pe, efon abami ti n sokunfa kokoro Zika ti ko gboogun ti wa ni Naijiria. Bakan naa lo si ro awon eniyan lati se ohun gbogbo ni ikapa won lati dena efon lati ma fenu kan won lara.

O ni awon eniyan le dena efon Zika yii nipa lilo neeti adena efon (mosquito nets) ni akoko ti won ba fe sun lale. “Ona abayo kan soso to wa bayii ni lilo mosquito nets lati daabo bo ara wa nitori wi pe, ko ti si oogun to le gba eniyan sile lowo arun kokoro Zika apani naa,” Ojogbon se alaye bee niluu Abuja.  Bakan naa lo gba awon alaboyun nimoran lati ma rin irin ajo lo awon agbegbe ti Zika ti n se ijamba lowolowo bayii latari ipo elege ti won wa.

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...