Home / Art / Àṣà Oòduà / “Ajo NFF kii ta agbaboolu soke okun” Aare NFF
nff

“Ajo NFF kii ta agbaboolu soke okun” Aare NFF

Ogbeni Amaju Pinnick to je aare ajo ti n risi ere boolu alafesegba, Nigeria Football Federation, ti fesi lati tako awon aheso kan ti n lo nigboro wi pe, ajo NFF n se bisineesi tita agbaboolu soke okun.

O ni iro to jina si otito ni aheso naa. Ninu oro re, o ni oseese ki awuyewuye naa jeyo ninu asigbo oro ti minisita fun ere idaraya ati awon odo, Ogbeni Solomon Dalung so.

O ni minisita so wi pe ki awon se kia nipa awon eto awon fun awon agbaboolu abele ti won fe lo maa gba boolu ni awon ilu okeere.

“A wa kii ta agbaboolu si okeere, iwe eri lasan ni awa n fi le won lowo. Mo si gba wi pe awon ti won gbe iroyin naa kiri ko gbo alaye minisita ye yekeyeke ni. Minista ko so nipa tita agbaboolu, awon eto wa lati se iranwo fun awon agbaboolu abele ti won fe lo si oke okun lo ni ka se ni kiakia,” Pinnick se alaye naa bee.

About admin

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...