Home / Art / Àṣà Oòduà / Enikan ti Buhari gbagbe lati fun ni ipo misita
enikan

Enikan ti Buhari gbagbe lati fun ni ipo misita

Ohun ti Ogbeni Yanju Adegboyega ko nipa maanu naa ni yii:

“Walaaahi!
Mo sese gbagbo loooto ni pe, alaimoore lo po julo ninu awon oloselu. Olorun n gbo, alaimoore ni Aare Buhari ati egbe oselu APC.
Eyin o gbagbo?

O daa naa, ipo minisita wo ni won fi okunrin yi, eni to f’emi ara re wewu lati fese rin lati ilu Eko lo siluu Abuja nitori ti Aare Buhari ati egbe oselu APC bori ibo.

Mo fe fi asiko fun aare orileede yii, Muhammadu Buhari ati egbe oselu APC ni gbedeke ojo meje lati wa ipo kan fun okunrin yii tabi ki won da ileese ijoba kan ti yoo maa ri si “Irin-are” sile. Ki won si fi maanu yi se olori re.

Bi bee ko! E ma jee ki n so nnkan ti yoo sele. Nitori, maa mobilaisi lati yo Ibadan kuro lara orileede Nigeria ni o.”

About admin

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...