Home / Art / Àṣà Oòduà / Ò̩pò̩ dúkìá sègbé sínú ìjàm̀bá iná ló̩jà Amu l’Ekoo
House-Fire

Ò̩pò̩ dúkìá sègbé sínú ìjàm̀bá iná ló̩jà Amu l’Ekoo

Ò̩pò̩ dúkìá sègbé sínú ìjàm̀bá iná ló̩jà Amu l’Ekoo
Láti o̩wó̩ Yínká Àlàbí
Eledua jowo maa so wa pelu ijamba ina to n sele lasiko eerun yii.
Lojiji ni ijamba tun be yo ni oja gbaju-gbaja Amu ti o wa ni ilu Mushin ni ipinle Eko.


Oja yii ni won ti n ta awon igi ikole,abesitoosi ikole ati awon ohun ikole miiran gbogbo.


Awon eso panpana tete de ibi isele yii sugbon epa ko boro ni oro ina naa. Gbogbo bi won se n da omi sii lo n da bii igba ti won da epo petiro si ina naa.
Dukia to le ni bilionu naira lo sofo sinu isele buruku naa, eni to kan lo mo.
Isele yii ba opo eniyan lokan je nitori pe ko si eni ton le mo oja yii tele to maa gbo pe ina joo guruguru ti ko ni kawo mori.
Ko tii si eda Olorun kan to le so ohun to fa ijamba ina naa nitori pe awon onise monamona ko muna wa ni gbogbo asiko naa.
Ki Eledua ba wa dawo aburu duro.

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...