Ní òní mo gbèrò láti tún ilé àti àyíká Adìe mi se, ni mo pàdé afayàfà yí, mo sá eré bí mo se le sa mo. Nítorí ìgbà àkókò mi rè é tí mà rí ejò ńlá báyìí láàyè, tí ...
Read More »Ogún-l’ógbòn àwon baba ńlá ìran yorùba l’ójé alágbára, lára won ni *Timi Àgbàlé olófà iná*.
Timi Àgbàlé, olóde tí ó sì jé jagunjagun tí Aláàfin rán lo sí ìlú Ede láti dáàbò bo àwon ènìyàn ibè. Alágbára ènìyàn ni Timi jé , tí a sì mò ó sí *Timi Àgbàlé olófà-iná*,gégé bí ìtàn se so, ...
Read More »Lobatan! The House of Saud bows to the House of Putin
Saudi Arabia pivots to Russia, the new sheriff in town by Pepe Escobar for the Asia Times What a difference a year – an eternity in geopolitics – makes. No one could see this coming; the ideological matrix of all strands of Salafi-jihadi ...
Read More »Alaafin decries attack on Yoruba culture by Islam & Christianity
By Daud Olatunji ABEOKUTA — The Alaafin of Oyo, Oba Lamidi Adeyemi, yesterday, raised the alarm over the erosion of Yoruba culture by what he called received religions of Islam and Christianity. Oba Adeyemi, Alaafin of Oyo The first class ...
Read More »Top 5 Most Arrogant Nigerian Celebrities in 2017 ?
You all know the 5 most humble celebrities in Nigeria today are the kind of Tuface, Don Jazzy, Genevieve Nnaji, Olamide and Funke Akindele all made the list since many humble ones in Naija…Well, listed here is 5 most arrogant ...
Read More »Physically challenged Nigerian woman weds her boo
A Physically challenged bride, wedded her boo, in a quiet wedding ceremony. A Nigerian Facebook user posted the couple’s wedding photos and wrote: “Weeping may endure for a night but joy cometh in the morning…who says you wouldn’t get married ...
Read More »Russian Military Releases Videos Showing Airstrikes On Isis Terrorists Entered Syria From Iraq
On October 10, the Russian Defense Ministry released videos showing airstrikes of the Russian Aerospace Forces on ISIS terrorists in the Syrian province of Deir Ezzor. According to the ministry, ISIS units entered Syria from Iraq thanks to a low ...
Read More »Odó kàyééfi ńlá tí ó wà ní *ADO AWAYE*.
Ìlú kéréje kan wà ní ìpínlè Oyo tí orúko ìlú náà sì ń jé *ADO AWAYE*, òdó kàyééfi kan wà ní ìlú yí tí ó jé wípé bí ènìyàn bá ti esè kan bo inú rè yóò fa eni náà ...
Read More »Òdómokùnrin odún mókàndílógún (19 years) fé odómobìnrin odún méèdógún (15 years) ní ilè àríwá (North) ní orílè èdè Nàìjíríà.
Àwòrán tí ó gba aféfé ni ti àwon tokotayà yí tí oko jé odún mókàndílógún tí ìyàwó sì jé odún méèdógún ní ilè àríwá orílè èdè Nàìjíríà. Ò n lò èro ayélujàra kan ni ó pín àwòrán tokotayà yí, tí ...
Read More »Àwon apàse ilé-ìwé Obafemi Awolowo University (OAU) pàse kí won mú àwon akékòó látàrí àtakò àláfíà (peaceful protest) tí won ń se.
Ogbà Obafemi Awolowo University (OAU) ti kó sí inú dàrúdàpò nígbà tí òpò akékòó tò lo sí àgó olóòpá tí ó wà ní Moore ní ìlú ile-ife láti bèèrè fún ìdásílè àwon akegbé won tí àwon ìgbìmò ìdábòbò Ogbà náà ...
Read More »