Home / Art / Àṣà Oòduà / Àgbàrá òjò ní ìlú Benin látàrí òjò nlá tí ó rò lánàá.

Àgbàrá òjò ní ìlú Benin látàrí òjò nlá tí ó rò lánàá.

Àgbàrá òjò ní ìlú Benin látàrí òjò nlá tí ó rò lánàá.

Ní òpópónà Uselu ní ìlú Benin ti ìpínlè Edo ni àgbàrá ti gbalè gbalé léyìn òjò ñlá tí ó rò . òpòlopò okò ti omi gbé lo, òpó àwon awakò ni omi gbé lo pèlú súgbón tí awon míràn fi esè fe.
Òpòlopò ònà tí èèyàn le rìn náà ni omi ti gbà tí kò sì se é rìn mó látàrí òjò tí ó fa àgbàrá ní gbogbo ìgbà.
Kódà òpò ilé tí ó wà ní ègbé òná bí ó se tò lo ní ojú ònà ni ó ti wólé.
Gégé bí a se gbó télè wípé omobìnrin kékeré kan ni òjò gbà ní owó ìyá rè ní ojú ònà yí náà, tí won kò sì rí osú rè láti bí òsè mélòó séyìn.
Èbé ni à ñ be àwon ìjoba kí won jòwó bá wa se nkan sí èyí, ñse ni ó dàbí eni wípé ó ti n di gbogbo ìgbà.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...