Home / Art / Àṣà Oòduà / Arákùnrin Oyinbo yí ló fé ìyàwó rè tí ó jé omo Edo, tí won sì se ìgbéyàwó ìbílè Alárédè.

Arákùnrin Oyinbo yí ló fé ìyàwó rè tí ó jé omo Edo, tí won sì se ìgbéyàwó ìbílè Alárédè.

Òyìnbó kò mà le mú ojú kúrò lórò lára àwon omoge orílè èdè Nìjíríà rárá, nítorí won mò wípé arewà ni won, won sì mo ìké oko se, bí kò bá jé béè ogún-l’ógbòn àwon òyìnbó ni ó ti fé omo orílè èdè Nìjíríà yí.
E wo arákùnrin yí níbi ayeye ìgbéyàwó ti ìbílè ti òun àti olorì rè, tí a kò bá rí kò omobìnrin náà rewà ó pò jú, e wo bí ó se dàbí eni wípé won bí Òyìnbó náà mó aso ìbílè náà ni.
Èyí wú ni lórí púpò.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...