Òyìnbó kò mà le mú ojú kúrò lórò lára àwon omoge orílè èdè Nìjíríà rárá, nítorí won mò wípé arewà ni won, won sì mo ìké oko se, bí kò bá jé béè ogún-l’ógbòn àwon òyìnbó ni ó ti fé omo orílè èdè Nìjíríà yí.
E wo arákùnrin yí níbi ayeye ìgbéyàwó ti ìbílè ti òun àti olorì rè, tí a kò bá rí kò omobìnrin náà rewà ó pò jú, e wo bí ó se dàbí eni wípé won bí Òyìnbó náà mó aso ìbílè náà ni.
Èyí wú ni lórí púpò.
 
		 Ọmọ Oòduà Naija Gist | News From Nigeria | Entertainment gist Nigeria|Networking|News.. Visit for Nigeria breaking news , Nigerian Movies , Naija music , Jobs In Nigeria , Naija News , Nollywood, Gist and more
Ọmọ Oòduà Naija Gist | News From Nigeria | Entertainment gist Nigeria|Networking|News.. Visit for Nigeria breaking news , Nigerian Movies , Naija music , Jobs In Nigeria , Naija News , Nollywood, Gist and more
				 
			

 
											 
											 
											 
											 
											
