Home / Art / Àṣà Oòduà / Àwòrán kí ó tó di ojó ìgbéyàwó tí ológun yí àti òdóbìnrin tí ó pàdé lórí èro ayélujára (Facebook) ya.

Àwòrán kí ó tó di ojó ìgbéyàwó tí ológun yí àti òdóbìnrin tí ó pàdé lórí èro ayélujára (Facebook) ya.

   Isé rí èro ayélujára n se kojá òye èdá…

Àwon oko pèlú Aya àfésónà yí ti setán láti di tokotayà ní òsè péréte si léyìn tí won làdé lórí èro ayélujára (Facebook). Gégé bí Ijeoma Nwosu se so, ó ní òun pàdé olólùfé òun Chukwuma Inya-Agha ní odún méta séyìn léyìn ìgbà tí ó ka èróngbà àwon èèyàn lórí oun tí ó pín ní orí (Facebook).
Báyìí won ti se tán àti féra ní ojó kesàn-án osù kejìlá (9/12/2017).

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Onibode

The Tale of Oníbodè Lálúpọn and the Dundun Drummer

Long ago, in the ancient city of Ibadan, famed for its warriors and sprawling hills, there lived a gatekeeper-warrior stationed in the outskirts of the city, in a settlement known as Lálúpọn on the way to Ìwó. His duty was clear: to watch the road, collect tolls, and guard the passage of traders and travellers entering and leaving Ibadan. Because of this important task, people called him Oníbodè Lálúpọn; the Gatekeeper of Lálúpọn. Though he was not particularly comely, Oníbodè ...