Home / Art / Àṣà Oòduà / Àwon onísé abe; bàbá kan ní orílé èdè Nàíjíríà àti omo rè obìnrin ti se isé abe lórí aláìsàn won .

Àwon onísé abe; bàbá kan ní orílé èdè Nàíjíríà àti omo rè obìnrin ti se isé abe lórí aláìsàn won .

Ò n lò èro ayélujára (Facebook) Bucandy Ayo Abubakar, tí ó jé onísé abe pín àwòrán ara rè àti bàbá rè àti bàbá rè onísé abe ti se isé-abe fún aláìsàn kan tí ó ní àìsàn “Appendix” ó sì ko síbè wípé .
“Nígbà tí bàbá re bá jé onísé abe ti ìwo náà sì jé ìgbákejì rè”.
Omo Àjànàkú kò le yàrá omo tí eyá bá bí eyá ní jo.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

yemoja 2026

Yoruba Yemoja float with 10,000 Litres of water by Mocidade Alegre Won the São Paulo Carnival 2026 in Brazil!

This majestic allegorical float, a viral sensation during the parade, featured Yemoja (Iemanjá) Yemoja was powerfully incorporated because the enredo “Malunga Léa – Rapsódia de uma Deusa Negra” was a heartfelt tribute to the late legendary Brazilian actress Léa Garcia (1930–2023). A pioneering African icon in theater, film, and TV (famous for roles like in Escrava Isaura and her work with Teatro Experimental do Negro). The theme celebrated her as a “deusa negra” (“Black” Goddess): her resilience, ancestral strength, female ...