Home / Art / Àṣà Oòduà / Àwòrán Saraki nígbà tí won se ìpàdé pèlú Woke, Ortom àti àwon míràn ni ìpínlè Kwara.

Àwòrán Saraki nígbà tí won se ìpàdé pèlú Woke, Ortom àti àwon míràn ni ìpínlè Kwara.

Àwon ìgbìmò tuntun rè é, Gómìnà ìpínlè River, Nyesom Ezenwo Wike tètè dé sí Ilorin ní ìpínlè Kwara fún ìpàdé pàtàkí náà pèlú àwon ti Benue náà, Gómìnà Samuel Ortom tí ó sèsè ko ìwé láti fi egbé APC sílè fún èyí tí a kò tí mò.
Sineto George Sekibo, Sineto Adawari pepple àti àwon míràn ni ó sin Gómìnà Wike lo sí ibi ìpàdé náà.
Àwon Gómìnà méjèèjì ti se ìpàdé pèlú Sineto Bukola Saraki àti Gómìnà ìpínlè Kwara, Abdul Fatah Ahmed.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...