Home / Art / Àṣà Oòduà / Davido, Gbajúgbajà olórin tí ó tún jé omo ebí Adeleke wo agbádá tí àwon egbé oní Àsìá se tí won sì ko orúko egbé won si.

Davido, Gbajúgbajà olórin tí ó tún jé omo ebí Adeleke wo agbádá tí àwon egbé oní Àsìá se tí won sì ko orúko egbé won si.

Olórin, tí ó tún jé òtòkùlú ti n se isé takuntakun láti ri dájú wípé, sínétò Ademola Adeleke di Gómìnà ìpínlè Òsun ní ibi ìdìbò tí ó n bò ní ojó àbáméta yí.

Ó tí è ti n sisé takuntakun láti polongo fún egbé PDP fún ègbón rè tí ó fé lo fún ipò gómìnà ní ojó àbámétà .
Èyí ni àwòrán ibi tí ó ti wo aso PDP fún Òsogbo ní ibi tí ó ti n polongo.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...