Home / Art / Àṣà Oòduà / Èèmò lukutu pébé ní ilé-èkó gíga ìfáfitì ti Ilé-ifè : Nígbà tí akékòó kan ya wèrè nígbà tí ó n kàwé lówó.

Èèmò lukutu pébé ní ilé-èkó gíga ìfáfitì ti Ilé-ifè : Nígbà tí akékòó kan ya wèrè nígbà tí ó n kàwé lówó.

Gégé bí a ti mo wípé òkan gbógì ní ilé-èkó gíga Òbafemi Awolowo University (OAU) jé ní orílè èdè Nìjíríà yí.

Sà déédéé ni a gbó wípé arábìnrin kan tí ó jé akékòó ilé-èkó yí ya wèrè látàrí ìwé kíkà nígbá yí ó jé wípé ìdánwò won ti kù sí dèdè.

Ní alé ìjeta ni ìsèlè yí selè, nígbá tí omobìnrin yí sa wèrè tán, ìwé tí ó n kà náà ló fi ñ lu ìlù. Àfi kí elédùà gbàwá ooo.

 

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...