Home / Art / Àṣà Oòduà / Ta Ni Elújoba?
Elújoba

Ta Ni Elújoba?

Elújoba ni gíwa tí ó kúrò
Lóríi oyè gégé bíi alásé oau
Láìpé yìí
Tí gbogbo ènìyàn sì n kan sárá sí òjògbòn náà
kìí kúkú se pé wón n déédé kan sáárá sí Baba
Ìwà rere àti òótó inú tí Baba
fi n sisé ló jé kí ójògbón ó gbayì lárà òtò
Omo Elújoba kò kò ju odún kan lo, kí ó tó san gbogbo 
owó àwon òsìsé tó n fa wàhálà kí ó tó gba èkù idà
ìyàlénu ni pé àwon tó ó tukò ogbà fémi télè fún bíi odún márùn-un séyìn won kò rí àseyorí kan tóka sí àmo ní géré tí òjògbón dé ìròrùn dé bá terútomo logba èyí tó kàmàmà ni pé
títí elújoba fi kúrò nípò àwon òsìsé kò dasé sílè rárá
ìtàn tí kò se gbàgbé nìyí nínú ogbà
Sé ó wá ye ká gbó pé irú eni rere béè ni àwon (efcc) wá lo fi sí àtìmó hmmmmm
ó rúmi lójú
oro yòrùbá sèsè wá yémi pe
aráyé ò fé òótó
èsùn tí wón fi kan Baba ni pé ó sanwó àwon òsìsé pèlú owó tí kìí se ti òsìsé
èyí ló mú kí àwon òsìsé ó bínú tí àwon akékòó náà sì gbarata pé kàkà kéku má je sèsé a ó fi sàwàdànu ni
Èyí ló fàá tí èèrò fi yabo ilé ejó tí wón sì n sòrò pèlú èdùn okán àti òpòlopò àkólé lówó tí ó so pé
E fi Elújoba sílè eni tó ye kí e mú, e ò mú u…..
hmmmmmmm
Àmó èmi mò pé fínni ni adìe n toko ìmó bò ni òrò náà yóò jé fun Elújoba
Ìdí tí mo fi be gègé lówè ni pé
ibò gan n lòrò Nigeria n lo?

*ODUNEWI PRODUCTION ..*

About ayangalu

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Onibode

The Tale of Oníbodè Lálúpọn and the Dundun Drummer

Long ago, in the ancient city of Ibadan, famed for its warriors and sprawling hills, there lived a gatekeeper-warrior stationed in the outskirts of the city, in a settlement known as Lálúpọn on the way to Ìwó. His duty was clear: to watch the road, collect tolls, and guard the passage of traders and travellers entering and leaving Ibadan. Because of this important task, people called him Oníbodè Lálúpọn; the Gatekeeper of Lálúpọn. Though he was not particularly comely, Oníbodè ...