Home / Art / Àṣà Oòduà / Ìgbà èdá

Ìgbà èdá

Ìgbà kò lo bí òréré
Ayé kò lo bí òpá ìbon,
Ìgbà kan ńlo
Ìgbà kan ńbo
Kí elédùmarè jé kí á n’ígbà tó dára n’ílé ayé wa

Ìgbà kan ni ogún náírà yí níyì púpò
Sùgbón nísìnín
Ó ti di ohun tí èèyàn ò fé rí mo.

Ìgbà rere ni kí á ma toro
Kí elédùmarè fún wa ní ìgbà òtun.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...