Home / Art / Àṣà Oòduà / Ìjo̩ba àpapò̩ t’ókun ló̩rùn Sowore àti Dasuki
Sowore

Ìjo̩ba àpapò̩ t’ókun ló̩rùn Sowore àti Dasuki

Ìjo̩ba àpapò̩ t’ókun ló̩rùn Sowore àti Dasuki
Lati owo
Yinka Alabi
Ijoba apapo orileede Naijiria ni o ti ni ki Ogbeni Omoyele Sowore ti o je oludari “iroyin ayelujara Sahara” ati Sambo Dasuki ti o je oluba-Aare damoran pataki (NSA) nigba isejoba Goodluck Jonathan maa wa jejo lati ile ni osan oni ojo kerinlelogun, osu kejila odun 2019.


Minisita eto idajo ni orileede yii, Abubakar Malami ni o gbe ejo naa kanri nigba ti ile ejo giga ti ni ki won maa wa jejo lati ile sugbon ti ijoba apapo ni ko dara ki a fi ina si ori orule sun.


Awuyewuye ti wa n po lori ejo naa ni orileede yii ati ile ibomiran.
Koda ija waye ni ana ode yii lori ki ijoba apapo le fi Sowore sile.


Abubakar Malami ni nigba ti ile ejo ti le ni kii won maa wa jejo lati ile pelu awon nnkan iduro won, to won si ti yege gbogbo nnkan naa, o ni ki won maa lo ile, ki won si ma se gbagbe adehun won.

iroyinowuro

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED FOOL in Your ancestral Land.

History 101: What it takes to be a MENTALLY ENSLAVED Harlequin in Your ancestral Land.

The quote for today is a page from Toyin Falola’s book, ‘Yoruba Warlords of the 19th Century’. To a lot of Yoruba Muslims. Islam means servitude to Usman Dan Fodio’s estate at Sokoto. They indulge in the same idiocy that led to the fall of the great Hausa civilization. Many Yoruba Muslims from Oyo are a dangerously brainwashed set of people that would pose future danger for the preservation of Yorubaland like their ancestors who pledged allegiance to Ilorin and ...