Home / Art / Àṣà Oòduà / Linda Ikeji padà so orúko baba omo rè, ó wípé Sholaye Jeremi ni baba omo òun àti oko tí n bò lónà.

Linda Ikeji padà so orúko baba omo rè, ó wípé Sholaye Jeremi ni baba omo òun àti oko tí n bò lónà.

Elétí Ofe, Linda Ikeji ti padà so baba omo rè, ó sì ti so wípé Sholaye Jeremi ni baba omo òun .

Ó tún so wípé orúko omo òun ni Jayce Jeremi , ó ko síbè wípé…
” mò n re’lé pèlú omo oba mi. Ìbèrè odún rere nínú ayé mi! Orúko rè a máa jé Jayce, Jayce Jeremi si ni yó ma jé.
N wó pín àwòrán láìpé”

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Onibode

The Tale of Oníbodè Lálúpọn and the Dundun Drummer

Long ago, in the ancient city of Ibadan, famed for its warriors and sprawling hills, there lived a gatekeeper-warrior stationed in the outskirts of the city, in a settlement known as Lálúpọn on the way to Ìwó. His duty was clear: to watch the road, collect tolls, and guard the passage of traders and travellers entering and leaving Ibadan. Because of this important task, people called him Oníbodè Lálúpọn; the Gatekeeper of Lálúpọn. Though he was not particularly comely, Oníbodè ...