Home / News From Nigeria / Breaking News / Mi ò ní dá DMs lóhùn mó – Davido so béè léyìn ìgbà tí ìkan nínú àwon olólùfé rè pa iró mo wípé òun ni ó kókó síde ìbáraenisòrò.

Mi ò ní dá DMs lóhùn mó – Davido so béè léyìn ìgbà tí ìkan nínú àwon olólùfé rè pa iró mo wípé òun ni ó kókó síde ìbáraenisòrò.

Ògá àkójopò HKN, Davido, tí ó pe ìkan lára àwon olólùfé rè obìnrin jáde, Sheilah Parker, tí ó gbe lo sí orí èro ayélujàra (snapchat ) láti p’aró mo wípé òun ni ó kókó síde ìbáraenisòrò pèlú arabìnrin náà. Olórin tí ó bèèrè wípé “Kílódé tí àwon ènìyàn fi rí báyìí? Ó tún jé kí won mò wípé òun kò ní dá àwon DMs lóhùn mó.
Àwòrán nìyí n’ísàlè….

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...