Home / Art / Àṣà Oòduà / Nìjíríà ìgbà wo ni a ó gba òmínira.

Nìjíríà ìgbà wo ni a ó gba òmínira.

Nìjíríà ńlé sunkún
Àwon èèyàn ibè ò ye é rérìn-ín òfò
Èrín òfò tí won rò pé ti ìdùnú ní se

Nìjíríà ìlú tí òmínira rè ti di omi ìnirà
Atún ti wálé
Ojó wo ni àwa náà yóò gba ife gbogbo àgbáyé
Ó mà se o!

Argentina tún ko bò wá láàná, won tún lé wa léré wálé láti odún 1995 ni wón kúkú ti ń fó wa lénu.

Ikò super Eagles ti láwon ò super mó oo A ti dágbére fún won ní Russia

Nìjíríà ìlú olómìnira.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Onibode

The Tale of Oníbodè Lálúpọn and the Dundun Drummer

Long ago, in the ancient city of Ibadan, famed for its warriors and sprawling hills, there lived a gatekeeper-warrior stationed in the outskirts of the city, in a settlement known as Lálúpọn on the way to Ìwó. His duty was clear: to watch the road, collect tolls, and guard the passage of traders and travellers entering and leaving Ibadan. Because of this important task, people called him Oníbodè Lálúpọn; the Gatekeeper of Lálúpọn. Though he was not particularly comely, Oníbodè ...