Home / Art / Àṣà Oòduà / Nìjíríà ìgbà wo ni a ó gba òmínira.

Nìjíríà ìgbà wo ni a ó gba òmínira.

Nìjíríà ńlé sunkún
Àwon èèyàn ibè ò ye é rérìn-ín òfò
Èrín òfò tí won rò pé ti ìdùnú ní se

Nìjíríà ìlú tí òmínira rè ti di omi ìnirà
Atún ti wálé
Ojó wo ni àwa náà yóò gba ife gbogbo àgbáyé
Ó mà se o!

Argentina tún ko bò wá láàná, won tún lé wa léré wálé láti odún 1995 ni wón kúkú ti ń fó wa lénu.

Ikò super Eagles ti láwon ò super mó oo A ti dágbére fún won ní Russia

Nìjíríà ìlú olómìnira.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...