Home / News From Nigeria / Breaking News / Odómokùnrin odún mókàndílógún (19years) tí ósì jí olóyè kan gbé ni owó tè ní ìpínlè River.

Odómokùnrin odún mókàndílógún (19years) tí ósì jí olóyè kan gbé ni owó tè ní ìpínlè River.

Àwon òlùgbógunti Adigunjalè ti ìpín Okehi ní ìpínlè River ni owó won te òdómokùnrin kan tí ó ń jé Emeka Nwala tí ó jé odún méèdógbòn (25years) àti òdómokùnrin Otamasiri Onyesu tí ó jé odún mókàndílógún. Tí won sì fi èsùn kan wón wípé àwon ni won jí olóyè pàtàkì kan gbé ní ìlú Umuehem tí won jí gbé pa mó fún òpòlopò ojó.
Àwon ìgbìmò oníwà rere ìlú ni ó s’ètò bí won se rí won mú nípa gbígbá rùkù ti àwon olóòpá púpò. Won ń ran àwon olóòpá lówó láti gbé won lo sí ilé-ejó láìpé…

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...