Don't Miss
Home / News From Nigeria / Breaking News / Odómokùnrin odún mókàndílógún (19years) tí ósì jí olóyè kan gbé ni owó tè ní ìpínlè River.

Odómokùnrin odún mókàndílógún (19years) tí ósì jí olóyè kan gbé ni owó tè ní ìpínlè River.

Àwon òlùgbógunti Adigunjalè ti ìpín Okehi ní ìpínlè River ni owó won te òdómokùnrin kan tí ó ń jé Emeka Nwala tí ó jé odún méèdógbòn (25years) àti òdómokùnrin Otamasiri Onyesu tí ó jé odún mókàndílógún. Tí won sì fi èsùn kan wón wípé àwon ni won jí olóyè pàtàkì kan gbé ní ìlú Umuehem tí won jí gbé pa mó fún òpòlopò ojó.
Àwon ìgbìmò oníwà rere ìlú ni ó s’ètò bí won se rí won mú nípa gbígbá rùkù ti àwon olóòpá púpò. Won ń ran àwon olóòpá lówó láti gbé won lo sí ilé-ejó láìpé…

About Awoyemi Bamimore

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Aláàfin Ọ̀yọ́ Has Been Crowned With Ade Ṣàngó

KABIYESI IKU BABA YEYE ALAAFIN ỌBA ABIMBỌLA OWOADE COMPLETED TRADITIONAL RITES AND EARNED HIS RESPECTIFÁ chose our ALAAFIN for us and now you can see he is following the tradition of his ancestors. If you do not know how powerful Alaafin is, check the crown on his head. This crown is believed to be very powerful. Ade Ṣàngó.This powerful crown must be given to Alaafin by Baba Mọ́gbà Sàngó who would place it on his head after completing the orò ...