Home / Art / Àṣà Oòduà / Òdómobìnrin tí ó gba òrékùnrin tè s’ílé nítorí wípé kò ní isé l’ówó bá pátá àti róbà ìdábòbò nínú ilé rè.

Òdómobìnrin tí ó gba òrékùnrin tè s’ílé nítorí wípé kò ní isé l’ówó bá pátá àti róbà ìdábòbò nínú ilé rè.

     Gégé bí ìtàn se so è yun-ùn tí won pín sí orí èro ayélujára (IG) ti Joro Olumofin. Òdómobìnrin tí ó gba òrékùnrin rè tí kò n’ísé l’ówó gbé nínú ilé rè ní Eko padà délé láti ìrìn-àjò tí ó lo láti ya òrékùnrin rè lénu sùgbón tí ó padà ri wípé n se ni omokùnrin náà n re je.

Gégé bí ó se so, òrékùnrin náà n fi tipátipà jé kí ó fi pátá tí ó won ìwòn mérìnlá (14) sílè fún oní ìwòn méwàá(10) sùgnón ìyàlénu lójé wípé obìnrin náà rí pátá tí ó won ìwòn méjìdínlógún nínú balùwè…

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...