Home / Art / Àṣà Oòduà / olópàá kan ní Enugu ti mú àwon òdóbìnrin méjì nígbà tí won n rìn l’ójú ònà látàrí aso ìwòkuwò tí won wò.

olópàá kan ní Enugu ti mú àwon òdóbìnrin méjì nígbà tí won n rìn l’ójú ònà látàrí aso ìwòkuwò tí won wò.

Gégé bí eni tí ojú rè to se so, tí ó sì gbe sí orí èro ayélujára se so, olópàá kan ní ìpínlè Enugu ni a ti fi èsùn kàn wípé ó mú àwon òdóbìnrin méjì tí won wò aso ìwòkuwò.
A gbó wípé ìsèlè yí selè ní ojó ajé (Monday), ogún’jó osù kokànlá (November 20) ní òpópónà Garrison ní Enugu.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

yemoja 2026

Yoruba Yemoja float with 10,000 Litres of water by Mocidade Alegre Won the São Paulo Carnival 2026 in Brazil!

This majestic allegorical float, a viral sensation during the parade, featured Yemoja (Iemanjá) Yemoja was powerfully incorporated because the enredo “Malunga Léa – Rapsódia de uma Deusa Negra” was a heartfelt tribute to the late legendary Brazilian actress Léa Garcia (1930–2023). A pioneering African icon in theater, film, and TV (famous for roles like in Escrava Isaura and her work with Teatro Experimental do Negro). The theme celebrated her as a “deusa negra” (“Black” Goddess): her resilience, ancestral strength, female ...