Home / Art / Àṣà Oòduà / Omoge kan ni owó tè tí won sì fi se èsín látárí wípé ó fo odi ilé onílé láti jí bisikitì .

Omoge kan ni owó tè tí won sì fi se èsín látárí wípé ó fo odi ilé onílé láti jí bisikitì .

       Ònlò èro ayélujárá ( Facebook) tí a mò sí Arc Pashal Chike Umeobi ló so wípé arábìnrin yí ni owó àwon figilanté tè ní Ezinifite , ìlú kan ní ìpínlè Anambra .

Arábìnrin yí ni won fi èsùn kàn wípé ó fo odi ilé láti jí ìpápánu tí a mò sí bisikitì ni owó pálábá rè bá ségi nígbà tí ìkan lára àwon figilanté ri wípé ògbòn n rùn, figilanté náà bá gbìyànjú àti mu sùgbón tí ó bó, ó sì yìn ìbon lùú tí ó sì yè é n ló bá tún fo odi ilé míràn láti balè nínú ilé onílé míràn ,kíá ni onílé yára figbe bonu, béè ni owó bá tè é….

About Awoyemi Bamimore

One comment

  1. Hardeymorlar Tozyne Thosco

    Haha……. O mu bisikiti, Haa……Ebi n pa niyen, Se ko jin pure water ni. (Olee……….)

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...