Home / Art / Àṣà Oòduà / ORÍLÈ ÈDÈ MI
Nigeria Flag

ORÍLÈ ÈDÈ MI

ORÍLÈ ÈDÈ MI

Nàìjíríà ìlú mi pàtàkì
Ìlú t’ókún fún ogbón
Pèlú òpòlopò àwon òjògbón
Ilé ogbón
Tí a ti n hun àgbòn ìwà ìbàjé
S’ogúndogójì di ààyò àwon òdó
Òsèlú di ohun wón k’èyìn sí
Egbé òsèlú di ìkan kò gbé’kan
“Birds of a feather”
Bí àwon olóyìnbó se máa n so
Iró n pa’ró fún iró
Ìtànje lásán làsàn
Ní àti ojó tí a ti gba òmìnira
Omi ìnira ni àwon olórí wa n fún wa mu
Màá se eléyìí
Màá se tòún
Sí bè…
Ìsé òun òsì
Kò tán ní àwùjo wa
Kílódé, kí ló se wá
PDP se ìjoba ó ya mó won lówó
APC ò sun wòn
Tani yóò gbà wá ní owó àwon jegúdú jerá wònyí
Tí wón n pe ra won ní olórí wa
Àkókò náà tó wàyìí
Ó tó géé oní bàtá kan kìí dá Orin
Èyin òdó, àsìkò náà ti tó
Láti GBA ìjoba
Ní owó àwon alágbára a tó kú má kùú a mònà òrun má lo
2019! E jé kí á dìbò fún
Òdó langba kí ìtèsíwájú leè
Dé bá gbogbo wa.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...