Home / Art / Àṣà Oòduà / Tánkà tí Ó gbiná ní ànà tí Ó sì pa òpò èèyàn.
bulava

Tánkà tí Ó gbiná ní ànà tí Ó sì pa òpò èèyàn.

Ní déédé agogo márùn-ún ìròlé àná ni ìjàmbá ńlá tí Ó tún jé mánigbàgbé fún orílè èdè Nìjíríà selè, nígbà tí Tánkà ńlá kan gbiná ní ojú pópó ònà tí ó wà láàrin ìlú Èkó si Ìbàdàn.

Òpò àwon èèyàn ni ókú tí àwon kan sì fi ara pa, ti Òpò okò sì sègbé.
Ó mà se o àfi kí olórun gbà wá ní orílè èdè yí.

Kí elédùmarè té àwon tí Óní kú sí aféfé rere.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...