Home / Art / Àṣà Oòduà / Timi Dakolo pín àwòrán ti ó rewà ti ìyàwó rè pèlú omo méta ní London.

Timi Dakolo pín àwòrán ti ó rewà ti ìyàwó rè pèlú omo méta ní London.

Gbajúgbajà olórin ti orílè èdè Nìjíríà, Timi Dakolo ti pín àwòrán ìyàwó rè àti àwon omo rè méta ní ìlú London, ó ko síbè wípé “wón tun ti dé baba wón tún ti dé”.

Timi Dakolo ti ó jé omo bíbí ìlú Accra ní orílè èdè Ghana tí baba rè sì jé omo Bayelsa ìlú kan ní orílè èdè Nìjíríà, orúko rè a máa jé David tí ìyá rè sí jé omo bíbí orílè èdè Ghana, orúko òun náà a máa jé Norah, tí ó kú nígbà tí Timi wà ní omo odún métàlá(13).

Bí ó tilè jé wípé omo bíbí orílè èdè Ghana ni Timi jé, tí ó sì tún ní ìwé omo ìlú ti orílè èdè Nìjíríà lówó, kò f’ìgbà kan so rí wípé omo ìlú méjì ni òun .

Njé èyí kò rewà bí?

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...