Home / Art / Àṣà Oòduà / Tope Osoba se ayeye ojó ìbí rè nígbà tí ó pé omo odún métàlélógbò (33) pèlú àwon àwòyanu àwòrán.

Tope Osoba se ayeye ojó ìbí rè nígbà tí ó pé omo odún métàlélógbò (33) pèlú àwon àwòyanu àwòrán.

Temitope Osoba tí gbogbo ènìyàn mò sí Tope Osoba jé òsèré orílè èdè Nìjíríà tí ó sì tún jé olùko eré, won bí i ní ojó kejì osù kejìlá, odún 1985.
Ó jé jé akékòó jáde ilé-èkó gíga ifáfitì Olabisi Onabanjo tí ó kó nípa èkó káràkárà.
Òsèré tí ó rewà yí bèrè eré orí ìtàgé ní odún 2005 nígbà tí ó kópa fún ìgbà àkókó nínú eré tí a mò sí “Ijoya” láti owó Laide Bakare.
Ó di gbajúgbajà òsèré ní odún 2009 nígbà tí ó kópa nínú “ogun mi” láti owó Dayo Amusan . Báyìí ó ti hàn nínú eré tí ó kojá ogún bí apeere, Abimbola, Anu oju mi láti owó Adesanya, Omotara Johnson, Gucci girl àti béè béè lo.
Ó se ayeye ojó ìbí rè pèlú àwon àwòrán tí ó ta lénu nígbà tí ó pé odún métàlélégbòn.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...