Home / Art / Àṣà Oòduà / Tope Osoba se ayeye ojó ìbí rè nígbà tí ó pé omo odún métàlélógbò (33) pèlú àwon àwòyanu àwòrán.

Tope Osoba se ayeye ojó ìbí rè nígbà tí ó pé omo odún métàlélógbò (33) pèlú àwon àwòyanu àwòrán.

Temitope Osoba tí gbogbo ènìyàn mò sí Tope Osoba jé òsèré orílè èdè Nìjíríà tí ó sì tún jé olùko eré, won bí i ní ojó kejì osù kejìlá, odún 1985.
Ó jé jé akékòó jáde ilé-èkó gíga ifáfitì Olabisi Onabanjo tí ó kó nípa èkó káràkárà.
Òsèré tí ó rewà yí bèrè eré orí ìtàgé ní odún 2005 nígbà tí ó kópa fún ìgbà àkókó nínú eré tí a mò sí “Ijoya” láti owó Laide Bakare.
Ó di gbajúgbajà òsèré ní odún 2009 nígbà tí ó kópa nínú “ogun mi” láti owó Dayo Amusan . Báyìí ó ti hàn nínú eré tí ó kojá ogún bí apeere, Abimbola, Anu oju mi láti owó Adesanya, Omotara Johnson, Gucci girl àti béè béè lo.
Ó se ayeye ojó ìbí rè pèlú àwon àwòrán tí ó ta lénu nígbà tí ó pé odún métàlélégbòn.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

policeman

Ọ̀gbẹ́ni Olaoye déèdé pòórá nílé ìtura kan nílùú Akure

Fẹ́mi Akínṣọlá Ádùrá tí a máa ń ṣe ni pé kí á má rin àrin f’ẹsẹ̀sí.Mọ̀lẹ́bí ọkùnrin kan, Ògbẹ́ni Olaoye Olatunde, tó jẹ́ igbákejì ọ̀gá àgbà ilé ẹ̀kọ́ girama kan nílùú Ọwọ ti ké gbàjarè pé ọkùnrin náà di àwárítì lẹ́yìn tó lọ fún idanilẹkọ ní ilé ìtura Sunview nílùú Akure. Iyawo arakunrin naa salaye rẹ pe, ni ọjọ kẹrinlelogun oṣu Kẹjọ, ọdun 2025, ni ọkọ rẹ dagbere pe ohun n lọ fun idanilekọ kan n’iluu Akure, eyi ti wọn ...