Home / Art / Àṣà Oòduà / “Ajo NFF kii ta agbaboolu soke okun” Aare NFF
nff

“Ajo NFF kii ta agbaboolu soke okun” Aare NFF

Ogbeni Amaju Pinnick to je aare ajo ti n risi ere boolu alafesegba, Nigeria Football Federation, ti fesi lati tako awon aheso kan ti n lo nigboro wi pe, ajo NFF n se bisineesi tita agbaboolu soke okun.

O ni iro to jina si otito ni aheso naa. Ninu oro re, o ni oseese ki awuyewuye naa jeyo ninu asigbo oro ti minisita fun ere idaraya ati awon odo, Ogbeni Solomon Dalung so.

O ni minisita so wi pe ki awon se kia nipa awon eto awon fun awon agbaboolu abele ti won fe lo maa gba boolu ni awon ilu okeere.

“A wa kii ta agbaboolu si okeere, iwe eri lasan ni awa n fi le won lowo. Mo si gba wi pe awon ti won gbe iroyin naa kiri ko gbo alaye minisita ye yekeyeke ni. Minista ko so nipa tita agbaboolu, awon eto wa lati se iranwo fun awon agbaboolu abele ti won fe lo si oke okun lo ni ka se ni kiakia,” Pinnick se alaye naa bee.

About admin

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Onibode

The Tale of Oníbodè Lálúpọn and the Dundun Drummer

Long ago, in the ancient city of Ibadan, famed for its warriors and sprawling hills, there lived a gatekeeper-warrior stationed in the outskirts of the city, in a settlement known as Lálúpọn on the way to Ìwó. His duty was clear: to watch the road, collect tolls, and guard the passage of traders and travellers entering and leaving Ibadan. Because of this important task, people called him Oníbodè Lálúpọn; the Gatekeeper of Lálúpọn. Though he was not particularly comely, Oníbodè ...