Home / Art / Àṣà Oòduà / “Ajo NFF kii ta agbaboolu soke okun” Aare NFF
nff

“Ajo NFF kii ta agbaboolu soke okun” Aare NFF

Ogbeni Amaju Pinnick to je aare ajo ti n risi ere boolu alafesegba, Nigeria Football Federation, ti fesi lati tako awon aheso kan ti n lo nigboro wi pe, ajo NFF n se bisineesi tita agbaboolu soke okun.

O ni iro to jina si otito ni aheso naa. Ninu oro re, o ni oseese ki awuyewuye naa jeyo ninu asigbo oro ti minisita fun ere idaraya ati awon odo, Ogbeni Solomon Dalung so.

O ni minisita so wi pe ki awon se kia nipa awon eto awon fun awon agbaboolu abele ti won fe lo maa gba boolu ni awon ilu okeere.

“A wa kii ta agbaboolu si okeere, iwe eri lasan ni awa n fi le won lowo. Mo si gba wi pe awon ti won gbe iroyin naa kiri ko gbo alaye minisita ye yekeyeke ni. Minista ko so nipa tita agbaboolu, awon eto wa lati se iranwo fun awon agbaboolu abele ti won fe lo si oke okun lo ni ka se ni kiakia,” Pinnick se alaye naa bee.

About admin

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...