Gégé bí a ti mò wípé eré bóòlù ife àgbáyé ńlo lówó. Ahmed Musa tí Ó jé òkan Lára àwon omo agbábòòlú Nìjíríà ti gbá bóòlù méjì òtòtò wo ilé àwon alátakò won tí a mò sí ikò Iceland.
Read More »
Awoyemi Bamimore Comments Off on Ahmed Musa ti mu Nìjíríà rérìn-ín ayò léèkan sí.
Gégé bí a ti mò wípé eré bóòlù ife àgbáyé ńlo lówó. Ahmed Musa tí Ó jé òkan Lára àwon omo agbábòòlú Nìjíríà ti gbá bóòlù méjì òtòtò wo ilé àwon alátakò won tí a mò sí ikò Iceland.
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Òrìsà tí ń darí aféfé
Oya òpèré, Ekùn oko asè’ké Oya má bá mi jà Mi ò l’ówó aféfé ńlé Èmi ò rí eni tí yó ràgàn, ràgàn bí Oya ní òde ìpo Kò séni tí ó ràgàn ràgàn bí Oya lótù ifé Oya lo ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Meet Paula Cristina Gomez – Cultural Ambassador, Alaafin Oyo
Àlàáfíà, Some days ago, The Ooni took his first official trip to Brazil, to connect with his subjects. According to a facebooker: ‘I got information for a very reliable source that the white, she-Devil called Paula Cristina Gomez, the self ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on E wá wo isé tí Àlùbósà.
_Sebí ohun tó bá jọnilójú, ni Yorùbá n sọ wí pé ó yanilẹ́nu. *Àwọn onímọ̀ ìjìnlẹ̀ sáyẹ́nsì kan ní ìlú CHINA ti jẹ́ kó yé wa wí pé ìwádìí tuntun tí fìdí rẹ̀ múlẹ̀ wí pé ÀLÙBỌ́SÀ (kò báà ṣe ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Eniyan koni rajo kofi orire kale sile ibiti aba koriwa mase pada leyinwa oo
Ori mi Apere isedami Ajifobi kan Amuni wale aye magbagbe Eni Orimi gbemi bose gbe omo alara tofidade owo isedami gbemi bosegbe omo ajero tofi tepaleke orimi gbemi bose gbe omo orangun ila tofidi eni apesin pitipiti mogbani Adurafun wape ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Ooni ti ile-ife ní ìdí òpe àgùnká .
Ayeye Odún ifá àgbáyé eléyìí tí ó wáyé ní òkè-ìtase ní ilú ilé-ifè. Ooni rèé ní ìdí òpe àgùnká ní ibi tí mùtúmùwà ti ń se àdúrà sí ìsèdá won, kódà oba náà kò jáfara.
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Ìwúre Òṣù Tuntun
Bí ÒṢÙ bá yọ loke terutọmọ niiri, omi ajipon kiiru, ninu ÒṢÙ kẹfa yi aye gbogbo wa yio toro minimini, bi Ọgẹdẹ ba pọn ará aa dẹẹ, ara oni ni emi àti Ìwọ oluka àtèjìṣẹ mi yi, àtijẹ atimu koni ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on A kú òsè jàkúta.
Sango oooo Olukoso ayanran ina Ina loju, ina lenu Sangiri, lagiri Olagiripapa figba edun bo Eefin ina la n da laye Ina nbe lodo oko mi lorun Abaabe ooooooooo Abaabe laba Se fun SANGO Emi Se SANGO labaabe Agbenajo, Agbenayan ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Àwòrán kí ó tó di ojó ìgbeyàwó tokotayà yí ti won pàdé nígbà tí won ń sin orílè èdè won lówó ní odún mérin séyìn.
Arábìnrin Nìjíríà kan tí a mò sí Rosemary nípa eni tí yó sèsè di oko rè Láìpé odún màrún-ùn séyìn, nígbà tí won ń sin orílè èdè won lówó ní Kaduna ti pín àwòrán kí ó tó di ojó ìgbeyàwó ...
Read More »Awoyemi Bamimore Comments Off on Fúlàní darandaran pa àwon èèyàn ní ojú ònà Makarda ní òpópónà Makarda.
Óní òun so gbangba gbàngbà ni Láì bèrù enikéni :báyìí ni Adamu Donald Dekwagh, wípé enikéni kò gbodò sùn nígbà tí igbákejì Ààre orílè èdè lo kí won ní Benue ní ànà yí tí àwon wòólì méjì àti darandaran pa. ...
Read More »
Ọmọ Oòduà Naija Gist | News From Nigeria | Entertainment gist Nigeria|Networking|News.. Visit for Nigeria breaking news , Nigerian Movies , Naija music , Jobs In Nigeria , Naija News , Nollywood, Gist and more