Home / Art / Àṣà Oòduà / Òrìsà tí ń darí aféfé

Òrìsà tí ń darí aféfé

Oya òpèré,
Ekùn oko asè’ké
Oya má bá mi jà
Mi ò l’ówó aféfé ńlé

Èmi ò rí eni tí yó ràgàn, ràgàn bí Oya ní òde ìpo
Kò séni tí ó ràgàn ràgàn bí Oya lótù ifé

Oya lo ràgàn ràgàn
Ló re nú ìgbé lò ké sí
Omo oyá d’olú
Oya mòdè ooo

Òpèré ní won ń jé
Òpéré ni won jé ó e
Gbogbo ilé olóya
Òpérè ni won je o e

Oya ní ìyá òun ò l’órogún
Óní òun náà ko ní l’óba kan
Òrìsà mérìndínlógún ni Oya bá n’ílé Sàngo gbogbo won ló fi eyin ojú lé lo. .

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Lati owo Aworosasa Moyo Okediji

Cultural War Rages on: Africa’s Civilizations Are Being Erased—who Will Teach African Artists?

AFRICAN AESTHETICS Many universities in the West are developing core curriculum programs focused on “Western Civilization,” while increasingly purging African, African Diaspora, Asian, and other civilizations from their programs. The West focusing on Western Civilization is appropriate. The days of African and African Diaspora Studies seem numbered. At the same time, Africana artists are producing contemporary works like never before. What are these Africana artists going to read? Are they going to study Western Civilization only, without any understanding of ...