Home / Art / Àṣà Oòduà / Raymond Dokpesi sé̩gun àrùn covid-19

Raymond Dokpesi sé̩gun àrùn covid-19

Raymond Dokpesi sé̩gun àrùn coronae̩i

Aja to rele Ekun to bo, o ye ki a kii ku ewu.
Gbajugbaju oludasile ileese redio ati telifison Ray power ati AIT ni o se alabapade ajakale arun coronavirus ni nnkan bii ose meji to koja lo.
Arun yii ko mu oun nikan, o tun mu mefa miiran ninu ebi re. Oni yii ni ori ko alagba naa yo pelu awon ebi re mefeefa.
Oluulu Naijiria, Abuja ni won ti ģba iwosan tiwon, ni ibi ti won ti n se itoju awon ti ajakale naa ba ko lu.


Gbogbo awon ebi, ore ati ojulumo lo ti bere si ni ki alagba naa ku oriire. Nitori pe aisan naa buru de bii wo pe ko mo olowo bee ni ko mo talaka sugbon Eledua ko won yo.

Ìròyìn láti o̩wó̩ Yínká Àlàbí

About ayangalu

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...