Home / Art / Àṣà Oòduà / Akeredolu bó̩ nínú àjàgà covid-19
Akeredolu

Akeredolu bó̩ nínú àjàgà covid-19

Akeredolu bó̩ nínú àjàgà covid-19

Ajakale arun coronavirus ti n pa eni kukuru, to n pa eni giga, ti ko mo olowo yato fun talaka, ko mo oba bee ni ko mo ijoye, ko ki n ja ija elesinmesin, ko si ohun to kan an pelu eleyameya.


Ajakale ohun naa lo ko lu odidi bii gomina mejo ni orileede yi, ni eyi ti Arakunrin Rotimi Akeredolu wa ninu won. Ose to koja lo kede funra re pe ayewo oun gbe arun coronavirus jade. Gomina yii ba lo fun iwosan, o bere si ni sise ofiisi nile.


Gomina yii naa lo tun kede ni irole oni pe ki a ba oun dupe nipa esi ayewo to tun jade lonii ti o si gbee pe aisan naa ti kuro ni ago ara Gomina Akeredolu.

Yínká Àlàbí

About AbubakarMuhd

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...