Home / Art / Àṣà Oòduà / Èmi ò ní fàá ká jáa pè̩lú Tinubu – Aregbesola
tinubu aregbesola

Èmi ò ní fàá ká jáa pè̩lú Tinubu – Aregbesola

Èmi ò ní fàá ká jáa pè̩lú Tinubu – Aregbesola

Gomina tele ri ni ipinle Osun, Ogbeni Rauf Aregbesola ni o tinsalaye ni aimoye igba pe oun ko ni Ojogbon kankan pelu Asiwaju Bola Tinubu.
O ni “ogede ko le wo koko ye tan,ko wa di igi buruku “.O ni Asiwaju lo gbe oun leyin, eewo tin nibi oun tun maa fi eyin naa gee je.

Aregbesola ni gbogbo ohun ti oun da lonii nidii oselu,ko seyin Asiwaju ati wo pe ojo tin ti pe ti awon tun ti jo n bo.

Orisiirisii egbe ni ijoba ibile Alimosho lo n salaye yii fun awon oniroyin pe, Aregbe ko Toledo fi igba Kan nii lokan lati idije du ipo Aare ni Osun 2923. Won ni Ogbeni Aregbe se maa wo kaa ile sun ko le dije du ipo pelu Tinubu layelaye.

Yínká Àlàbí

About ayangalu

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Asiwaju Bola Ahmed Tinubu

Presidential Broadcast – President Tinubu chastised Fubara five times over the Rivers problem.

In accordance with Section 305 of the “1999 Constitution (The constitution, which we still operate, is Decree 24 and was promulgated into law by a military dictator General Abdusalam Abubakar, on May 5, 1999, and has become operative from May 29, 1999 till date), President Bola Tinubu has proclaimed a State of Emergency in Rivers State. After the situation in Rivers intensified to include pipeline vandalism and the bombing of the Transamadi pipeline, an emergency meeting with service chiefs and ...