Fìdáù Ajímọ̀bi, ẹbí nìkan ní wọ́n ń retí–Ẹbí Ajímọ̀bi Ṣé wọ́n ní kìí jẹ́ ti baba t’ọmọ, kó mọ́ ní ààlà. Èyí ló díá fún bí àwọn ẹbí olóògbé Abíọ́lá Ajímọ̀bi tí sàlàyé pé ,kí àwọn olùkẹ́dùn, ó má wulẹ̀ ...
Read More »
ayangalu Comments Off on Fìdáù Ajímọ̀bi, ẹbí nìkan ní wọ́n ń retí–Ẹbí Ajímọ̀bi
Fìdáù Ajímọ̀bi, ẹbí nìkan ní wọ́n ń retí–Ẹbí Ajímọ̀bi Ṣé wọ́n ní kìí jẹ́ ti baba t’ọmọ, kó mọ́ ní ààlà. Èyí ló díá fún bí àwọn ẹbí olóògbé Abíọ́lá Ajímọ̀bi tí sàlàyé pé ,kí àwọn olùkẹ́dùn, ó má wulẹ̀ ...
Read More »ayangalu Comments Off on È̩yin òsìsé̩ mi nílò àyè̩wò coronavirus kíákíá- Akeredolu
È̩yin òsìsé̩ mi nílò àyè̩wò coronavirus kíákíá – Akeredolu Arakunrin Rotimi Akeredolu ti o je gomina ipinle Ondo lo n gba awon alabasise re niyanju ki won fi oro ti oun se arikogbon. O ni iba lasan ni o se ...
Read More »ayangalu Comments Off on Àwo̩n aké̩kò̩ó̩ ti lè wo̩lé, mótò ti lè rìn làti ìpínlè̩ sí ìpínlè̩ – NCDC
Àwo̩n aké̩kò̩ó̩ ti lè wo̩lé, mótò ti lè rìn làti ìpínlè̩ sí ìpínlè̩ – NCDC Ijoba apapo ti fowo si aba ti awon ajo NCDC gbe lo si odo Aare. Ijoba fi aaye sile ki awon ara ilu maa rin ...
Read More »ayangalu Comments Off on Keyamu àti àwo̩n Asojú sòfin tutó̩ sí ara wo̩n lójú
Keyamu àti àwo̩n Asojú sòfin tutó̩ sí ara wo̩n lójú Minisita fun ipinle ati eto ise ni orileede yii, Agbejoro agba Festus Keyamu ni awon Asoju sofin ranse si ni ilu Abuja lonii. Won fi saarin, won si bere si ...
Read More »ayangalu Comments Off on Mí ò ì pinnu lóri ìdíje Ààrẹ ọdún 2023-Tinubu
Mí ò ì pinnu lóri ìdíje Ààrẹ ọdún 2023-Tinubu Báá ti ṣe làá wí, ẹnìkan kìí yan àna rẹ̀ lódì ni Yorùbá wí àsamọ̀ yìí ló díá fún bí asáájú ẹgbẹ́ òṣelú ẹgbẹ́ APC, Sẹ́nétọ̀ Bola Ahmed Tinubu tí ṣọ ...
Read More »ayangalu Comments Off on Ògún Majek wọ káà ilẹ̀ sùn
Ògún Majek wọ káà ilẹ̀ sùn Ọlọ́jọ́ ń kajọ́, ẹ̀dá ò fiyè si.Ìjọ ọmọ tuntun dáyé, nijọ́ ìdùnnú, ẹ̀rín, òhun ọ̀yàyà fún ẹbí,ará, pẹ̀lú ìyekan. Ṣùgbọ́n kìí rọgbọ ká sàdédé sàfẹ̀kù èèyàn ẹni pékú yọwọ́ ọ rẹ̀ ní dúníyàn. Àsamọ̀ ...
Read More »ayangalu Comments Off on Abiola Ajimobi sùn un re
Ikú pàgbẹ̀ àṣírí aláró tú.Ikú pàlùkò àbùkù kará ìkosùn.Ọrùn má kánjú, gbogbo wa la dágbádá ikú.Ìgbà átàsìkò ẹ̀dá ló só kùnkùn.Gíńgín ladáhunṣe tó mewé e re.Gbogbo wa lòpè nípa àkúnlẹ̀yàn.Òkú ń sunkú òkú, akáṣọlérí ń sunkú ara a wọn.Sùn un ...
Read More »ayangalu Comments Off on Abọ ìwádìí yóó ṣọ pàtó ikú tó pàwọn òṣìṣẹ́ wa– Àjọ FRSC
Abọ ìwádìí yóó ṣọ pàtó ikú tó pàwọn òṣìṣẹ́ wa– Àjọ FRSC Ìlú u gángan lọ̀pọ̀ ìṣẹ̀lẹ̀ láyé,n Iàwọn àgbà se ṣọ pé,ẹ̀yìn ló kọ sẹ́nìkan, n tó kọjú sẹ́lòmíìn.Bí a kò bá gbàgbé, àìpẹ́ yìí ni ìṣẹ̀lẹ̀ ajániláyà pàtì ...
Read More »ayangalu Comments Off on INEC kọ lẹ́tà APC láti ṣe ìbò abẹ́nú l‘Ondo
INEC kọ lẹ́tà APC láti ṣe ìbò abẹ́nú l‘Ondo Ṣé àwọn àgbà ní bí eégún kò bá ṣe n tó tóbi, atọ́kùn rẹ̀ kìí tú ìdí rẹ̀ wò. Àjọ olómìnira tó ń ṣe kòkárí ètò ìdíbò Orílẹ̀ yìí tí fọnmú ...
Read More »ayangalu Comments Off on Colourful Photos: The Olowo of Owo Kingdom
His Imperial Majesty, Alaiyeluwa Oba Ajibade Gbadegesin Ogunoye III, The Olowo of Owo and Paramount Ruler of Owo KingdomPicture: Igogo festival 2019 See more photos bellow
Read More »
Ọmọ Oòduà Naija Gist | News From Nigeria | Entertainment gist Nigeria|Networking|News.. Visit for Nigeria breaking news , Nigerian Movies , Naija music , Jobs In Nigeria , Naija News , Nollywood, Gist and more