MC Oluo̩mo̩ fo̩wó̩ o̩lá gbáwa lójú – NURTWLáti o̩wó̩ Yínká ÀlàbíOro ti gbogbo ara ilu ni o ti ku regbe ti o si ti di ohun igbagbe ni o tun n rugbo ni ibere ise yii laarin Musiliu Akinsanya ati ...
Read More »This is what we call Pálapàla in Ede Oodua.
Sacrilege! This man is standing up and shaking hands with the ALÁÀFIN Ọ̀YỌ̀. They say he is from Bahia. Why is he shaking hands with the Alaafin? Because he is old enough to do so? This is what we call ...
Read More »Awujale changes the rule: No more secret cult burial for Obas
Awujale… Asks people to flog osugbo The Awujale and Paramount ruler of Ijebuland Oba Dr. Sikiru Kayode Adetona who also doubles as the President of the Ijebu Traditional Council may have set to clash with traditional worshipers otherwise called ‘Osugbo’ ...
Read More »Ìjọba ti ayédèrú ilé ọmọ aláìlóbìí pa, ọmọdé mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n gbòmìnira
Ìjọba ti ayédèrú ilé ọmọ aláìlóbìí pa, ọmọdé mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n gbòmìnira Fẹ́mi Akínṣọlá Àwọn aláṣẹ tọ́rọ̀ kan lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti kó àgádágodo sílẹ̀kùn ilé ọmọ aláìóbìí kan tí kò ní wè é òfin ní ìpínlẹ̀ Kaduna, tí wọ́n sì tú ọmọdé ...
Read More »Àwọn ará ilú dáná sún èèyàn méjì tí wọ́n furasí bíi olè
Àwọn ará ilú dáná sún èèyàn méjì tí wọ́n furasí bíi olè Ọjọ́ gbogbo n t’olè, ọjọ́ kan n tolóhun.Àwọn ènìyàn méjì kan ti wọ́n fura si gẹ́gẹ́ bi olè, ni wọ́n ti dáná sun nílùú Calabar, tíí ṣe olú ...
Read More »#Amotekun: Thank God FG Is Not Averse To Community Policing ― Ooni
The Ooni of Ife, Oba Enitan Adeyeye Ogunwusi commended the Federal Government of Nigeria for its stand on community policing. The Ooni of Ife also reserved special praises for southwest governors for putting aside political differences in finding a lasting ...
Read More »Ẹgbẹ́ Shiites wọ́de l’Abuja, wọ́n jó Àsìá Amẹ́ríkà
Ẹgbẹ́ Shiites wọ́de l’Abuja, wọ́n jó Àsìá Amẹ́ríkà Egbìnrìn ọ̀tẹ̀, bá a se n pàkan, nìkan ń rúÀwọ́n ọmọ ẹgbẹ́ “Islamic Movement of Naigeria” (IMN) tí gbogbo ènìyàn mọ sí Shi’ites lọ́jọ́ ajé ti ya sí ìgboro lágbègbè ilé ìtajà ...
Read More »Traditionists need 5 public holidays like Christians and Muslims too
The allegations and counter allegations by the two dominant religious body - Muslims and Christians is a worrisome issue that every Nigerian should be concerned about. In this opinion, Aanu Adegun, writes on the need to allow traditionalists have their own holidays if the two religious truly want fairness, equity and justice as they claimed.
Read More »Ẹjẹ yóó sàn, bí Amẹ́ríkà ṣe pa olórí ọmọ ogun un wa – lran
Ẹjẹ yóó sàn, bí Amẹ́ríkà ṣe pa olórí ọmọ ogun un wa..lran Kójú má ríbi , gbogbo ara lòògùn rẹ̀,bó ṣe jẹ́ pé, ó ń bọ̀ ,ó ń bọ̀ , gbogbo ara ní wọ́n mú tó o.À bí kí lọ̀rọ̀ ...
Read More »È̩ ń fi ẹ̀wọ̀n run imú ẹ̀yin Olóyè Ìbàdàn mọ́kànlélógún tẹ ń ǹ pera a yín lọ́ba
Ọrọ̀ kò tíì tán lórí àwọn Olóyè mọ́kànlélógún tí Ilé ẹjọ́ sọ pé kí wọ́n lọ rọọ́kún nílé nílùú Ìbàdàn. Kọmíṣọ́nnà ètò ìdájọ́ tẹ́lẹ̀rí nípìńlẹ̀ Oyo, Ọ̀gbẹ́ni Michael Lànà ló ṣe ìkìlọ̀ fún wọn pé, kí wọ́n yé pe ara ...
Read More »