Home / News From Nigeria / Breaking News (page 127)

Breaking News

Àwòrán kí ó tó di ojó ìgbéyàwó olùwòsàn tí ó tún lóyún sínú àti oko rè tó jé Engineer.

Àwòrán kí ó tó di ojó ìgbéyàwó olùwòsàn tí ó tún lóyún sínú àti oko rè tó jé Engineer. Olúwòsàn tí ó tún lóyún sínú àti oko rè tí ó jé Engineer ti pín àwòrán kí ó tó di ojó ...

Read More »

Àwòrán omo odún mókàndínlógún (19) tí won mú pèlú orísirísi èyà ara ní Awka.

Gégé bí ìròyìn se so, won ti fi ìgò gún omo odún mókàndínlógún (19) yánmayànma látàrí àwon èyà ara tí won bá ní owó rè, won bá omoníka àti ojú ara omo odún mérin okùnrin ní Awka, ìpínlè Anambra. Afura ...

Read More »

Tonto Dikeh se tán láti se isé abe láti tún ara rè dá.

Tonto Dikeh se tán láti se isé abe láti tún ara rè dá. Gbajúgbajà àti ìlú mòóká òsèré tí a mò sí ìyá ìjo, Tonto Dikeh, ti gbe lo sí orí èro ayélujára Ínsítágírámú láti jé kí ámò wípé nse ...

Read More »

KÁDÀRÁ Ò GBÓÒGÙN

Adáni wáyé ti dáni sáyé ná. Káwayé máyà tó sayé dàwáàlọ. Òréré layé kò see wò tán. Àyàfi ká gba kádàrá lókù. Kádàrá ò seé kọ̀ láìgbà. Ádíá f’ẹ́ja tó f’ibú selé. Ádíá f’ọ́pọ̀lọ́ tó f’òkè s’ebùgbé. Ọ̀pọ̀ló f’omi s’elé, ...

Read More »

Olódùmarè mà tóbi lóba ooo.

Olódùmarè mà tóbi lóba ooo. Kíni olórun olódúmarè kò le se tán, Olódùmarè tó dá ayé òhun òrun tí ó sì so òrò sí órìlè ayé, òrò náà á máa jé Ifá tí ó fi rán òrúnmìlà baba àgbónìrègún. Òdú ...

Read More »

Oro Agba from Omololu Olunloyo, a Governor of Oyo State under the NPN

Dr. Omololu Olunloyo, a former Governor of Oyo State under the NPN said “I won’t lie to you, I wasn’t in Awolowo’s Party but I respect him a lot. I would enter his house in Oke Ado and drink beer, ...

Read More »
S 300 Syria

S-300 in Syria – a preliminary assessment

[This article was written for the Unz Review] We now know a little more about which version of the S-300 family the Russians have delivered to the Syrians: the Russians have converted a number of S-300PM and S-300P2 systems to the ...

Read More »

Photos: Ibrahim Suleiman And Linda Ejiofor’s Traditional Wedding

Nollywood actress, Linda Ejiofor becomes legally and traditionally married with her love, actor Ibrahim Suleiman. See photos from the traditional wedding:

Read More »

Olorì Basirat tí ó pé odún mókàndínlógún ni ojó mélòó séyìn ya àwon àwòrán tí ó wuyì.

Olorì oba àti ìyá ìbejì ni a gbó wípé ó máa n dá oba lóhùn láàfin àti wípé òhun ni ó máa n pèsè gbogbo nkan tí Kábìèsí fé láàfin àti ní orí èro ayélujára. A gbó wípé kò sí ...

Read More »

Òsèré Yvonne Jegede àti Oko è kí omo tuntun káàbò tí ó tún jé àkóbí won.

Gbajúgbajà Òsèré Yvonne Jegede Fawole àti oko rè dun nú nígbà tí won bí omo tuntun tí ó tún jé Àkóbí won. Bí ó ti lè jé wípé a kò tí mò bóyà ako ni àbí abo sùgbón a mò ...

Read More »

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb