Home / Art / Àṣà Oòduà / Àgbàrá òjò ti gbalé gbalè ní ìlú ilé-ifè ní àná tí Òpò akékòó kò sì rí àyè lo sí ilé-èkó.

Àgbàrá òjò ti gbalé gbalè ní ìlú ilé-ifè ní àná tí Òpò akékòó kò sì rí àyè lo sí ilé-èkó.

   Gégé bí a ti mò wípé ilé-ifè jé ìlú tí ilé-èkó gíga wà, tí ó sì kún fún àwon akékòó bíi àwon akékòó ilé-èkó gíga ifáfitì ti Obafemi Awolowo university (OAU) àti ilé-èkó gíga ifáfitì ti Oduduwa university ilé-ifè (OUI).

Yorùbá bò wón ní àgbàrá òjò kò ní òhun kò n’ílé wó sebí onílé ni kò ní gbà fun, àgbàrá òjò eléyìí ti w’olé nítorí àwon ará ilé ti gbaa láyè tí ó pò.
E má jé kí á k’ólé s’ójú àgbàrá mó a kò a ò gbó, kí á má dalè sí ojú àgbàrá mo, a kò a ò gbà. Erù àwon akékòó tó sòfò ló pò, ìwé èrí àwon míràn tilè ti bómi lo .
Kí elédùmarè sàánú wa , kí ó má jé kí á ríjà omi.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Omisore

Àwàdà kẹrí-Kẹrì ni àwọn kọmití tó ní mi ò lè díje du ipò gómìnà APC ni 2026 n ṣe – Omisore

Yínká Àlàbí Awọn kọmiti to n ṣe àyẹ̀wò awọn oludije du ipo gomina labẹ ẹgbẹ́ oselu APC ti ja igbakeji gomina tẹlẹ ni ipinle Osun, Alagba Iyiola Omisore ati awọn mẹfa miiran.Wọn ni iwe wọn ko pe lati dije du ipo gomina ipinlẹ naa. Awọn mẹfẹẹfa to ku naa ni – Babatunde Oralusi, Oyedotun Babayemi, Dr. Akin Ogunbiyi, Benedict Alabi, Adegoke Rasheed Okiki, ati Senator Babajide Omoworare.Iyiola Omisore ni awada Kẹri-Kẹri ni awọn kọmiti naa n se nitori ti wọn ...