Home / Art / Àṣà Oòduà / Simi kúnlè ní orí ìtàgé láti kí ògbóntarìgì olórin tí a mò sí Lágbájá, nígbà Ó ń dá àwon èèyàn lárayá lówó.

Simi kúnlè ní orí ìtàgé láti kí ògbóntarìgì olórin tí a mò sí Lágbájá, nígbà Ó ń dá àwon èèyàn lárayá lówó.

Simi tí síde ayeye tí Jannie, Jazz àti Whisky pè ní ìlú Abuja ní alé ojó náà, Simisola jungle ní orí ìtàgé láti kí eni ńlá, èníyàn pàtàkí àti gbajúgbajà olórin láti dá àwon èníyàn lárayá papò.

Ògbóntarìgì olórin tí Ó máa n gbé eégún tí èyí kà láyà náà kúnlè láti fa Simi sókè tí ó sì fà á móra láti gbe dìde.
Simi tí Ó pín àwòrán yí sí orí èro ayélujára tí a mò sí instagram rè, tí Ó sì ko síbè pé “àlá mi wá sí ìmúse láti pàdé gbajúgbajà olórin yí láti dá àwon èníyàn lárayá papò.

” lánàá mo pàdé ògbóntarìgì olórin, ìlú mòóká, mo sì gbádùn ayé mi” báyìí ni Simisola wi.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...