Home / Art / Àṣà Oòduà / Ajimobi àti Yinka Ayefele pàdé níbi ayeye Àádòrún odún (90) ojó-ìbí Olúbàdàn.

Ajimobi àti Yinka Ayefele pàdé níbi ayeye Àádòrún odún (90) ojó-ìbí Olúbàdàn.

Ajimobi àti Yinka Ayefele pàdé níbi ayeye Àádòrún odún (90) ojó-ìbí Olúbàdàn.
Ìyàlénu ñlá gbáà ni ayeye Àádòrún ojó-ìbí olúbàdàn ti ilè ìbàdàn tí a mò sí Oba Saliu Akanmu Adetunji ní ojó Àìkú.
Gómìnà ìjoba ìpínlè Oyo Abiola Ajimobi lo síbi ayeye Àádòrún odún ojó-ìbí Olúbàdàn tí ìyàwó rè sìn ín lo, ìyàwó rè tí a mò sí Mrs. Florence Ajimobi, Gómìnà ìpínlè Oyo télè náà lo èyun-ùn Adebayo Alao-Akala; Teslim Folarin náà kò gbéyìn àwon míràn náà sì péjú síbè.
Gbajúgbajà olórin Yinka Ayefele náa lo síbi ayeye ojó-ìbí náà tí ó sì hàn wípé inú rè ñ dùn gan kòdá nígbá tí ó rí Ajimobi inú rè tún dùn gan, èyí hàn ní ojú rè púpò bí ó tilè jé wípé won sèsè wó ilé-isé rè tí ó rún owó ribiribi sí ni tí òpò sì ba kédùn .
Ayeye tí ó wú ni lórí yîí ni Oònirìsà, Oba Adeyeye Enitan tún lo síbè náà tí àwon oba míràn náà sì péjú síbè bíi Oba Eleruwa ti Èrúwà, Oba Samuel Adegbola; Olugbo ti Igbo; Oba Obateru Akinrintan àti Obanikoro láti èkó, tí ó wá sojú Oba Èkó, Oba Rilwan Akinolu.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Onibode

The Tale of Oníbodè Lálúpọn and the Dundun Drummer

Long ago, in the ancient city of Ibadan, famed for its warriors and sprawling hills, there lived a gatekeeper-warrior stationed in the outskirts of the city, in a settlement known as Lálúpọn on the way to Ìwó. His duty was clear: to watch the road, collect tolls, and guard the passage of traders and travellers entering and leaving Ibadan. Because of this important task, people called him Oníbodè Lálúpọn; the Gatekeeper of Lálúpọn. Though he was not particularly comely, Oníbodè ...