Home / Art / Àṣà Oòduà / Ajimobi àti Yinka Ayefele pàdé níbi ayeye Àádòrún odún (90) ojó-ìbí Olúbàdàn.

Ajimobi àti Yinka Ayefele pàdé níbi ayeye Àádòrún odún (90) ojó-ìbí Olúbàdàn.

Ajimobi àti Yinka Ayefele pàdé níbi ayeye Àádòrún odún (90) ojó-ìbí Olúbàdàn.
Ìyàlénu ñlá gbáà ni ayeye Àádòrún ojó-ìbí olúbàdàn ti ilè ìbàdàn tí a mò sí Oba Saliu Akanmu Adetunji ní ojó Àìkú.
Gómìnà ìjoba ìpínlè Oyo Abiola Ajimobi lo síbi ayeye Àádòrún odún ojó-ìbí Olúbàdàn tí ìyàwó rè sìn ín lo, ìyàwó rè tí a mò sí Mrs. Florence Ajimobi, Gómìnà ìpínlè Oyo télè náà lo èyun-ùn Adebayo Alao-Akala; Teslim Folarin náà kò gbéyìn àwon míràn náà sì péjú síbè.
Gbajúgbajà olórin Yinka Ayefele náa lo síbi ayeye ojó-ìbí náà tí ó sì hàn wípé inú rè ñ dùn gan kòdá nígbá tí ó rí Ajimobi inú rè tún dùn gan, èyí hàn ní ojú rè púpò bí ó tilè jé wípé won sèsè wó ilé-isé rè tí ó rún owó ribiribi sí ni tí òpò sì ba kédùn .
Ayeye tí ó wú ni lórí yîí ni Oònirìsà, Oba Adeyeye Enitan tún lo síbè náà tí àwon oba míràn náà sì péjú síbè bíi Oba Eleruwa ti Èrúwà, Oba Samuel Adegbola; Olugbo ti Igbo; Oba Obateru Akinrintan àti Obanikoro láti èkó, tí ó wá sojú Oba Èkó, Oba Rilwan Akinolu.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

“Ìyálóde, Eléékò & The Heavenly Companions: Discover the Mysterious Classes of Egbe in Yoruba Tradition”

Classes of Egbe (Heavenly Mate of Every Human) Also known as Alaragbo in some areas of Yoruba land, Egbe is generally more associated with children than with adults according to Eji-Ogbe. Based on the character traits of human on Earth, the Yoruba have classified Egbe into different categories. Ìyálóde Ìyálóde is regarded as the leader of Egbe on Earth. Leadership quality is most evident characteristic of this class of Egbe. Going by the name, it may appear that only females ...