Home / Art / Àṣà Oòduà / Sineto Musiliu Obanikoro ti lo kí Oònirìsà .

Sineto Musiliu Obanikoro ti lo kí Oònirìsà .

Sineto Musiliu Obanikoro ti lo kí Oònirìsà .

Sineto Musiliu Obanikoro tí ó jé adarí àwon olúdábòòbò ti orílè èdè Nìjíríà télè ti lo kí baba wa Oònirìsà tí a mò si àrólé odùduwà ní ìlú ilé-ifè ní ojó mélòó séyìn.

Èyí fi hàn wípé kò sí bí èèyàn se le tó Oba ba lórí ohun gbogbo, bí ó ti le wú kí ènìyàn bí olá tó Oba ni oba yóò máa jé.
Obanikoro dòbálè tán pátápátá fún baba wa Adeyeye Enitan Ogunwusi. Àwòrán rèé ní ìsàlé.

About Awoyemi Bamimore

VI

Viral Video

Support Ooduarere

SUPPORT OODUARERE
Scan QR code below to Donate Bitcoin to Ooduarere
Bitcoin address:
1FN2hvx5tGG7PisyzzDoypdX37TeWa9uwb
x

Check Also

Lati Ọwọ Aworosaṣa Moyọ Okediji

Cultural War Rages on: Africa’s Civilizations Are Being Erased—who Will Teach African Artists?

AFRICAN AESTHETICS Many universities in the West are developing core curriculum programs focused on “Western Civilization,” while increasingly purging African, African Diaspora, Asian, and other civilizations from their programs. The West focusing on Western Civilization is appropriate. The days of African and African Diaspora Studies seem numbered. At the same time, Africana artists are producing contemporary works like never before. What are these Africana artists going to read? Are they going to study Western Civilization only, without any understanding of ...